Ọjọ́ méje ti pẹ́ jù láti wá ojútùú sí ìnira tí owó Náírà ń kóbá ará ìlú – Afenifere sí Buhari

Oríṣun àwòrán, Collage 5 Èrèlè 2023 Ẹgbẹ́ Afenifere ilẹ̀ Yorùbá ti sọ fún Ààrẹ Muhammadu Buhari…

Read More

Amosun bẹ̀rẹ̀ ìpoloǹgò ìbò fún olùdíje ADC, sọ̀rọ̀ tako Abiodun

5 Èrèlè 2023 Gomina ana nipinlẹ Ogun, Ibikunle Amosun, ti fẹsun kan gomina to wa nipo,…

Read More

Amẹ́ríkà já bàlúù aṣòfófó China lórí òkun Atlantic

Oríṣun àwòrán, Reuters 5 Èrèlè 2023 Orilẹede Amẹrika ti ja baluu alafẹfẹ (baloon) orilẹede China kan,…

Read More

“Vandi bèèrè ọ̀tá ìbọn mìíràn lọ́wọ́ mi torí ọta ìbọn rẹ̀ kó pé mọ́ lẹ́yìn ikú Bolanle Raheem”

Oríṣun àwòrán, Others 2 Èrèlè 2023 Ọkan lara awọn Ọlọpa to n jẹri nibi igbẹjọ to…

Read More

Ọ̀pọ̀ owó Naira tuntun ń bẹ lọ́wọ́ àwọn agbébọn, yẹ̀yẹ́ ni wọn ń fi Emefiele ṣe – Gumi

Oríṣun àwòrán, Screen shot 2 Èrèlè 2023 Àyípadà Naira kò tu irun kan lára àwọn agbébọn,…

Read More

Wo ohun àràmàndà tí àwọn olósèlú máa ń ṣe lásìkò ìbò láti fa ojú olùdìbò mọ́ra

28 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Èrèlè 2023 Oríṣun àwòrán, Collage Lati…

Read More

Ènìyàn kan kú bí ìwọ́de lórí ọ̀wọ́n gógó owó Náírà ṣe tẹ̀síwájú nílùú Ibadan lónìí

3 Èrèlè 2023 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Èrèlè 2023 Ní òwúrọ̀ ọjọ́ Àbámẹ́ta…

Read More

Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Kwara da àwọn ọlọ́pàá sí báǹkì lórí ọ̀wọ́ngógó Náírà

Oríṣun àwòrán, CBN 4 Èrèlè 2023 Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kwara ti kéde pé àwọn ti da…

Read More

INEC bẹ̀rẹ̀ dídán ẹ̀rọ BVAS wò ṣáájú ètò ìdìbò gbogbogboò

Oríṣun àwòrán, Others 4 Èrèlè 2023 Àjọ to n ri si eti idibo Naijiria, INEC ti…

Read More

Ẹ wo orílẹ̀-èdè tí àlùbọ́sà ti wọ́n ju ẹran lọ

Oríṣun àwòrán, ROLEX DELA PENA/EPA-EFE/REX/Shutterstock 4 Èrèlè 2023 Kaakiri awoͅn orileͅede kọọkan ni agbaye ni aluboͅsa…

Read More